Bí wọ́ n ṣe pàṣẹ pé kí wọn fi kùkùté àti gbòǹgbò igi náà sílẹ̀ , èyí túmọ̀ sí wí pé a ó dá ìjọba rẹ padà fún ọ lẹ́ yìn ìgbà tí o bá ti mọ̀ wí pé, Ọ̀run jẹ ọba (Dáníẹ́ lì 4:26).
Bíbélì sọ, nínú Dáníẹ́ lì 4, sọ nípa bí Nebukadinésárì ṣe lá àlá kan tó dà á láàmú gan-an. Nínú àlá yìí, ó rí igi àgbàyanu kan tó ga tó sì lágbára, tó ń pèsè ibi ààbò àti oúnjẹ fún gbogbo ẹ̀ dá alààyè. Bí ó ti wù kí ó rí, wọ́ n pàṣẹ fún áńgẹ́ lì kan pé kí wọ́ n gé igi náà lulẹ̀ , kí wọ́ n sì fi kùkùté kan ṣoṣo tí a fi irin àti idẹ dè síle ̣ ̀ . Àlá yìí mú kí ọkàn ọba dàrú, ó sì kàn sí Dáníẹ́ lì, wòlíì Ọlọ́ run, láti túmọ̀ rẹ̀ .
Dáníẹ́ lì ṣí i payá pé ọba fúnra rẹ̀ ni igi náà, òun yóò rẹsílẹ̀ nítorí ìgbéraga re ̣ ̀ títí òun yóò fi gbà pé "ọ̀ run je ̣ ́ ọba" (Dáníẹ́ lì 4:26). Ọdún kan lẹ́ yìn náà, tí Nebukadinésárì kò tíì ronú pìwà dà, Nebukadinésárì; ó sì di wèrè fún ọdún méje, ó gbé bí ẹranko, ó ń jẹ koríko, ó sì ń rìn kiri nínú oko.
Gẹ́ gẹ́ bí Dáníẹ́ lì 4:17 ti sọ,pr àṣẹ yìí wá láti ọ̀ dọ̀ "àwọn olùṣọ́ " pé: ‘Olùṣọ́ ni ó gbé ìpinnu náà jáde, àṣẹ sì wá láti ọ̀ dọ̀ ẹni mímọ́ , kí gbogbo alààyè le mọ̀ wí pé, Ọ̀gá-ògo ni olórí ìjọba ènìyàn, ó sì ń fi fún ẹnikẹ́ ni tí ó wù ú, òun sì ń gbé onírẹ̀ lẹ̀ lórí i wọn." À̀wọn " olùṣọ́ " níhìn-ín ń tọ́ ka sí àwọn ẹ̀ dá áńgẹ́ lì tí a yàn láti bójú tó ọ̀ ràn lórí ilẹ̀ ayé, pẹ̀ lú ọlá àṣẹ láti fipá mú ìfẹ́ Ọlọ́ run.
Nebukadinésárì rò pé òun ń ṣàkóso ayé, títí tí a fi fipá mú mú un láti jẹ́ wọ́ ìṣàkóso ọ̀ run. Ó rí bá kanna lónìí. Àwọn tí wọ́ n fi irọ́ pípa sọ pé wọ́ n ní ọlá àṣẹ pípé lórí àwọn ẹlòmíràn, tí wọ́ n ń ṣiṣẹ́ lábẹ́ ẹ̀ tàn pé ipa tí wọ́ n ní, fún wọn ni agbára ìdarí lórí àwọn orílẹ̀ -èdè, wọn ò mọ̀ pé ọlá àṣẹ tòótọ́ wà pẹ̀ lú Ọlọ́ run àti Ìjọba Rẹ̀ ti ọ̀ run. Gbogbo agbára je ̣ ́ ti Olúwa, Ó sì ńse àwọn idajọ Rẹ lórí ile ̣ ̀ ayé nípasẹ̀ Ì̀ jọ: “Jésù si wá sọ fun wọn, wipe, Gbogbo agbára ni ati fi fún mi ní ọ̀ run àti ní ayé.” (Máttíù 28:18).
A fi agbára mú ìfẹ́ Ọlọ́ run sẹ nínú ayé wa: “èyí tí ó fi sínú Kristi, nígbà tí o ti jí dìde kúrò nínú òkú, tí ó sì mú un jókòó lọ́ wọ́ ọ̀ tún nínú àwọn ọ̀ run. Ó gbéga ju gbogbo ìjọba, àti àṣẹ, àti agbára, àti òye àti gbogbo orúkọ tí a ń dá, kì í ṣe ni ayé yìí nìkan, ṣùgbọ́ n ni èyí tí ń bọ̀ pẹ̀ lú. Ọlọ́ run sì ti fi ohun gbogbo sábẹ́ ẹsẹ̀ rẹ̀ , ó sì fi í ṣe orí lórí ohun gbogbo fún ìjọ, èyí tí i ṣe ara rẹ̀ , ẹ̀ kúnrẹ́ rẹ́ ẹni tí ó kún ohun gbogbo ní gbogbo ọ̀ nà.” (Éfésù 1:20-23). Halleluyah!